Jump to content

Nikki Laoye

Lát'ọwọ́ Wikipedia, ìwé ìmọ̀ ọ̀fẹ́
Nikki Laoye
Nikki Laoye àti Kirk Franklin lórí ìtàgé ní ọdún 2009
Nikki Laoye
Background information
Orúkọ àbísọOyenike Laoye
Ọjọ́ìbí19 Oṣù Kejìlá 1980 (1980-12-19) (ọmọ ọdún 43)
Lagos, Nigeria
Ìbẹ̀rẹ̀Osun State, Nigeria
Irú orin
Occupation(s)
  • Singer
  • songwriter
  • media personality
  • actress
  • humanitarian
InstrumentsVocals
Years active2005–present
LabelsWahala Media Entertainment
Websitereverbnation.com/nikkilaoye/nikkilaoye

Oyenike Laoye, tí a mọ iṣẹ rẹ sí agbohùn olórin sílẹ̀, olórin ní,ẹnití o máa ṣe ohun kan fún àwọn ènìyàn , o máa n ko orin sí lè , oníjó, òṣèré ní. Tí a mọ̀ ipa takuntakun tí òun kò nínú orin , atí eré orí ìtàgé.[1] Gẹ́gẹ́ bí agbohùn olórin sílè, ilé iṣé orin Laoye o tí gbà ọ̀pọ̀lọpọ̀ àmì ẹ̀yẹ bí Obìnrin tó dáńgájiá nínú orin kíkọ ní ọdún 2013[2] àti All African Music Awards (AFRIMA) ní ọdún 2014 fún Best Female Artiste in African Inspirational Music.[3][4] Ó gbajúmọ̀ fún orin tó kọ ní ọdún 2006, tí àkọ́lé rẹ̀ jẹ́ Never felt this Way before, orin oníjó ti ọdún 2013 "1-2-3", orin "Only You", èyí tí ó kọ pẹ̀lú Seyi Shay ní ọdún 2006 àti orin Onyeuwaoma pẹ̀lú Banky W.[5]

Àwọn ìtọ́kasí

[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]
  1. "10,000 Lagosians rock Inspiration FM praise jam". Vanguard Newspaper (Lagos, Nigeria). 1 January 2010. http://www.vanguardngr.com/2010/01/10000-lagosians-rock-inspiration-fm-praise-jam//. 
  2. Osaz, Tony (27 December 2013). "Olamide wins big @ Headies 2013 + full list of winners". Vanguard (Lagos, Nigeria). https://www.vanguardngr.com/2013/12/olamide-wins-big-headies-2013-full-list-winners/. 
  3. Ade, Ola (15 November 2015). "AFRIMA The Chips Go Down Tonight". Vanguard (Lagos, Nigeria). https://www.vanguardngr.com/2015/11/afrima-awards-the-chips-go-down-tonight/. 
  4. Showemimo, Dayo (31 December 2014). "AFRIMA award is Nikki Laoye's 5th in 2014". TheNet Newspaper (Lagos, Nigeria). http://thenet.ng/2014/12/afrima-award-is-nikki-laoyes-5th-in-2014/. 
  5. Adesida, Olumide (14 February 2016). "MUSIC: Nikki Laoye feat. Banky W – Onyeuwaoma". TheNet Newspaper (Lagos, Nigeria). http://thenet.ng/2016/02/music-nikki-laoye-feat-banky-w-onyeuwaoma/.